a
Gẹ 46.8-27
;
Nu 26.4-50
.
Exodus 1:1-4
A ni àwọn ọmọ Israẹli lára
1
a
Ìwọ̀nyí ni àwọn orúkọ ọmọ Israẹli tí wọ́n bá Jakọbu lọ sí Ejibiti, ẹnìkọ̀ọ̀kan pẹ̀lú ìdílé rẹ̀:
2
Reubeni, Simeoni, Lefi àti Juda;
3
Isakari, Sebuluni àti Benjamini;
4
Dani àti Naftali;
Gadi àti Aṣeri.
Copyright information for
YorBMYO